Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Lóde òní, ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú Kirisẹ́ńdọ̀mù ló kọ̀ láti lo orúkọ Jèhófà, àní wọ́n tiẹ̀ yọ ọ́ kúrò nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ẹ̀dà ìtumọ̀ Bíbélì. Àwọn kan ń fi àwọn èèyàn Ọlọ́run ṣẹlẹ́yà nítorí pé wọ́n ń lo orúkọ Ọlọ́run. Síbẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn èèyàn yìí ló ń fi ìtara ìsìn lo gbólóhùn náà, “Halelúyà,” tó túmọ̀ sí “Ẹ yin Jáà.”