Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Bíbélì sọ pé: “Jèhófà kò sí nínú ẹ̀fúùfù náà . . . , ìmìtìtì ilẹ̀ náà . . . , [àti] iná náà.” Àwọn ìránṣẹ́ Jèhófà yàtọ̀ sáwọn abọ̀rìṣà tí wọ́n máa ń jọ́sìn afẹ́fẹ́, iná tàbí òjò. Jèhófà lágbára gan-an, torí náà kò lè wà nínú àwọn nǹkan tóun fúnra ẹ̀ dá.—1 Àwọn Ọba 8:27.