Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
d Nínú Òfin Mósè, Ọlọ́run béèrè pé: “Ṣé ó yẹ kí o gbógun ti igi inú igbó bí ẹni ń gbógun ti èèyàn ni?” (Diutarónómì 20:19) Nígbà tí Júù kan tó ń jẹ́ Philo, tó jẹ́ ọ̀mọ̀wé ní ọgọ́rùn-ún ọdún kìíní ń ṣàlàyé òfin yìí, ó sọ pé: “Táwọn èèyàn bá ń jà, tí wọ́n wá lọ ń fìkanra mọ́ àwọn nǹkan tó wà láyìíká wọn láìṣe pé àwọn nǹkan náà ṣẹ̀ wọ́n, ìwà àìtọ́ ni wọ́n hù yẹn” lójú Ọlọ́run.