ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

d Nínú Òfin Mósè, Ọlọ́run béèrè pé: “Ṣé ó yẹ kí o gbógun ti igi inú igbó bí ẹni ń gbógun ti èèyàn ni?” (Diutarónómì 20:19) Nígbà tí Júù kan tó ń jẹ́ Philo, tó jẹ́ ọ̀mọ̀wé ní ọgọ́rùn-ún ọdún kìíní ń ṣàlàyé òfin yìí, ó sọ pé: “Táwọn èèyàn bá ń jà, tí wọ́n wá lọ ń fìkanra mọ́ àwọn nǹkan tó wà láyìíká wọn láìṣe pé àwọn nǹkan náà ṣẹ̀ wọ́n, ìwà àìtọ́ ni wọ́n hù yẹn” lójú Ọlọ́run.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́