Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Ọ̀rọ̀ Gíríìkì tá a tú sí “wá àlàáfíà” túmọ̀ sí “kí àwọn tó ń bára wọn ṣọ̀tá pa dà di ọ̀rẹ́.” Torí náà, ohun tí ẹni tó ń wá àlàáfíà fẹ́ ṣe ni pé kó gbìyànjú láti ran ẹni tó ṣẹ̀ lọ́wọ́, tó bá ṣeé ṣe, kí ẹni náà lè mú gbogbo ohun tó ń bí i nínú kúrò lọ́kàn.—Róòmù 12:18.