Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Àwọn tó ń ṣèwádìí ìtumọ̀ àwọn ọ̀rọ̀ inú Bíbélì sọ pé ọ̀rọ̀ Hébérù yìí “jẹ́ kó hàn kedere pé kì í ṣe ọ̀rọ̀ ṣíṣé aláboyún léṣe nìkan lọ̀rọ̀ náà túmọ̀ sí.” Ẹ máà tún gbàgbé pé Bíbélì ò sọ bí oyún náà ṣe gbọ́dọ̀ dàgbà tó kẹ́ni tó jẹ́ kó wálẹ̀ tó lè rí ìdájọ́ mímúná Jèhófà.