Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Nígbà tó yá, a yan Pọ́ọ̀lù láti jẹ́ “àpọ́sítélì fún àwọn orílẹ̀-èdè,” àmọ́ kò sígbà kan tí wọ́n kà á mọ́ àwọn Méjìlá náà. (Róòmù 11:13; 1 Kọ́r. 15:4-8) Pọ́ọ̀lù ò kúnjú ìwọ̀n láti ní àǹfààní àrà ọ̀tọ̀ yẹn torí pé kò sí lára àwọn tó tẹ̀ lé Jésù nígbà tí Jésù ń ṣe iṣẹ́ òjíṣẹ́ rẹ̀ láyé.