Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Nínú àwọn àkọsílẹ̀ míì, Bíbélì sọ nípa àjíǹde ọmọdé àti àgbà, ọkùnrin àti obìnrin àti tàwọn ọmọ Ísírẹ́lì àti àjèjì. O lè kà nípa wọn nínú 1 Àwọn Ọba 17:17-24; 2 Àwọn Ọba 4:32-37; 13:20, 21; Mátíù 28:5-7; Lúùkù 7:11-17; 8:40-56; Ìṣe 9:36-42; 20:7-12.