Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Jẹ́nẹ́sísì 4:26 sọ pé nígbà ayé Énọ́ṣì tó jẹ́ ọmọ ọmọ Ádámù, “àwọn èèyàn bẹ̀rẹ̀ sí í pe orúkọ Jèhófà.” Àmọ́, ẹ̀rí fi hàn pé wọ́n ń lo orúkọ náà lọ́nà tí kò tọ́, ó ṣeé ṣe kí wọ́n máa fi orúkọ Jèhófà pe àwọn òrìṣà wọn.
b Jẹ́nẹ́sísì 4:26 sọ pé nígbà ayé Énọ́ṣì tó jẹ́ ọmọ ọmọ Ádámù, “àwọn èèyàn bẹ̀rẹ̀ sí í pe orúkọ Jèhófà.” Àmọ́, ẹ̀rí fi hàn pé wọ́n ń lo orúkọ náà lọ́nà tí kò tọ́, ó ṣeé ṣe kí wọ́n máa fi orúkọ Jèhófà pe àwọn òrìṣà wọn.