Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Àwọn kan lè gbàdúrà sí Jesu nítorí pé wọ́n gbàgbọ́ pé òun ni Ọlọrun. Ṣùgbọ́n Ọmọkùnrin Ọlọrun ní Jesu jẹ́, òun fúnraarẹ̀ sì jọ́sìn Jehofa, Bàbá rẹ̀. (Johannu 20:17) Fún ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ àlàyé síi lórí kókó-ẹ̀kọ́ yìí, wo Iwọ Ha Nilati Gbàgbọ́ Ninu Mẹtalọkan Bí?, tí a tẹ̀jáde láti ọwọ́ Watchtower Bible and Tract Society of New York, Inc.