Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ àwọn àkọsílẹ̀ wà tí a lè kẹ́kọ̀ọ́ nínú wọn, láti inú àwọn àpẹẹrẹ tí ó tẹ̀lé e yìí, kíyèsí ohun tí ìwọ fúnraàrẹ lè kọ́ nípa Jesu tí ó lè fikún ìṣọ̀kan nínú ìjọ rẹ: Matteu 12:1-8; Luku 2:51, 52; 9:51-55; 10:20; Heberu 10:5-9.