ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

a Nígbà tí Bibeli sọ pé “ohun yòówù tí ènìyàn bá ń fúnrúgbìn, èyí ni oun yoo ká pẹlu,” èyí kò túmọ̀sí pé ìjìyà ẹnì kan gbọ́dọ̀ jẹ́ ìyà-ibi láti ọ̀dọ̀ Ọlọrun. (Galatia 6:7, NW) Nínú ayé ti Satani jọba lé lórí yìí, àwọn olódodo sábà máa ń dojúkọ ìṣòro púpọ̀ ju àwọn ènìyàn burúkú lọ. (1 Johannu 5:19) Jesu sọ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé: “Ẹ̀yin yoo sì jẹ́ ohun ìkórìíra lọ́dọ̀ gbogbo ènìyàn nítìtorí orúkọ mi.” (Matteu 10:22, NW) Àìsàn àti irú àwọn àgbákò mìíràn lè ṣe ẹnikẹ́ni nínú àwọn olùṣòtítọ́ ìránṣẹ́ Ọlọrun.—Orin Dafidi 41:3; 73:3-5; Filippi 2:25-27.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́