Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Ìwé náà Palestine in the Time of Christ sọ pé: “Nínú àwọn ọ̀ràn kan, obìnrin ni a wò bí ọgbọọgba pẹ̀lú ẹrú. Fún àpẹẹrẹ, kò lè jẹ́rìí ní ilé-ẹjọ́, yàtọ̀ sí láti jẹ́rìí sí ikú ọkọ rẹ̀.” Ní títọ́ka sí Lefitiku 5:1, ìwé The Mishnah ṣàlàyé pé: “[Òfin nípa] ‘ìbúra ìjẹ́rìí’ kan ọkùnrin ṣùgbọ́n kì í ṣe obìnrin.”—Shebuoth 4:I.