Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Òpìtàn Júù ọ̀rúndún kìn-ínní Josephus ròyìn pé Salome arábìnrin Ọba Herodu rán ọkọ rẹ̀ ní “àkọsílẹ̀ kan tí ń tú ìgbéyàwó wọn ká, èyí tí kò bá òfin àwọn Júù mu. Nítorí ọkùnrin (nìkan) ni a fàyè gbà láti ṣe èyí.”—Jewish Antiquities, XV, 259 [vii, 10].