Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a “Ìtàn Ọbabìnrin Ṣébà tẹnu mọ́ ọgbọ́n Sólómọ́nì, ọ̀pọ̀ ìgbà ni a sì ti pè é ní ìtàn àròsọ (1 Ọb. 10:1-13). Ṣùgbọ́n, àyíká ọ̀rọ̀ náà fi hàn pé, ìbẹ̀wò rẹ̀ sọ́dọ̀ Sólómọ́nì ní í ṣe ni ti gidi pẹ̀lú òwò, nítorí náà, ó bọ́gbọ́n mu; kò sí ìdí láti ṣiyèméjì nípa òtítọ́ ìtàn náà.”—Ìwé gbédègbẹ́yọ̀ The International Standard Bible Encyclopedia (1988), Ìdìpọ̀ IV, ojú ìwé 567.