Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Josephus ròyìn pé àwọn ará Róòmù tí ń kọluni náà yí ìlú náà ká, wọ́n wa yàrà yí apá kan odi ìlú náà ká, kí wọ́n dáná sun ẹnubodè tẹ́ńpìlì Jèhófà ló kù. Èyí fa ìbẹ̀rùbojo láàárín àwọn Júù tí a sé mọ́ inú rẹ̀, nítorí tí wọ́n ti rí i pé ikú ti dé.—Wars of the Jews, Ìwé Kejì, orí 19.