ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

b Òfin mìíràn tó tún jọ pé ó yẹ fún àfiyèsí sọ pé ọkùnrin tí ẹ̀yà ìbímọ rẹ̀ bá ti bà jẹ́ kò gbọ́dọ̀ wọ ìjọ Ọlọ́run. (Diutarónómì 23:1) Àmọ́ o, ìwé náà, Insight on the Scriptures sọ pé, dájúdájú “èyí ní í ṣe pẹ̀lú mímọ̀ọ́mọ̀ tẹni lọ́dàá fún ète àtiṣe ìṣekúṣe, irú bíi bíbá ẹ̀yà kan náà lò pọ̀.” Nítorí náà, òfin náà kò kan ọ̀ràn ìfètòsọ́mọbíbí. Ìwé Insight tún sọ pé: “Lọ́nà tó tuni nínú, Jèhófà sọ tẹ́lẹ̀ nípa àkókò tóun yóò tẹ́wọ́ gba àwọn ìwẹ̀fà gẹ́gẹ́ bí ìránṣẹ́ òun, bí wọ́n bá sì ṣègbọràn, wọn yóò ní orúkọ tó sàn ju àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. Nígbà tí Jésù Kristi mú Òfin kúrò, gbogbo èèyàn tó bá ń lo ìgbàgbọ́, láìka ipò wọn àtẹ̀yìnwá sí, ló lè di ọmọ Ọlọ́run nípa tẹ̀mí. A ti mú àwọn ìyàtọ̀ ti ẹran ara kúrò.—Aísá 56:4, 5; Jòh 1:12.”

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́