Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Ní àwọn àkókò tí a kọ Bíbélì, sísin òkú ẹnì kan jẹ́ ohun tí wọ́n kà sí pàtàkì gan-an ni. Nítorí náà, fífi irú ìsìnkú bẹ́ẹ̀ du ẹnì kan sábà máa ń jẹ́ àbùkù gbáà, ó sì fi hàn pé irú ẹni bẹ́ẹ̀ ti kùnà ojú rere Ọlọ́run.—Jeremáyà 25:32, 33.