Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
d Fún àpẹẹrẹ, Fíníhásì yára kánkán láti dá àrùn lùkúlùkú tó pa ẹgbẹẹgbàárùn-ún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì dúró, Dáfídì sì gba àwọn ẹmẹ̀wà rẹ̀ tí ebi ti fẹ́rẹ̀ẹ́ lù pa níyànjú láti dara pọ̀ mọ́ òun nínú jíjẹ búrẹ́dì àfihàn tó wà nínú “ilé Ọlọ́run.” Kò sí èyí tí Ọlọ́run dẹ́bi fún pé ó jẹ́ ìkùgbù nínú ọ̀ràn méjèèjì yìí.—Mátíù 12:2-4; Númérì 25:7-9; 1 Sámúẹ́lì 21:1-6.