Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn Kristẹni ẹni àmì òróró ni Róòmù 12:1 tọ́ka sí ní pàtó, ìlànà tó wà níbẹ̀ kan “àwọn àgùntàn mìíràn” pẹ̀lú. (Jòhánù 10:16) Àwọn wọ̀nyí “ti dara pọ̀ mọ́ Jèhófà láti máa ṣe ìránṣẹ́ fún un àti láti nífẹ̀ẹ́ orúkọ Jèhófà, láti lè di ìránṣẹ́ fún un.”—Aísáyà 56:6.