Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Kókó náà pé ọ̀rọ̀ Hébérù fún “ọgbọ́n” sábà máa ń jẹ́ ọ̀rọ̀ táa ń lò fún obìnrin kò tako bí a ṣe lo ọgbọ́n láti dúró fún Ọmọ Ọlọ́run. Ọ̀rọ̀ táa ń lò fún obìnrin ni a tún lò fún ọ̀rọ̀ Gíríìkì náà “ìfẹ́” nínú gbólóhùn tó sọ pé “Ọlọ́run jẹ́ ìfẹ́.” (1 Jòhánù 4:8) Síbẹ̀ a lò ó láti tọ́ka sí Ọlọ́run.