Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Bó tilẹ̀ jẹ́ pé Josephus sọ pé àwọn Júù kò tàbùkù sí àwọn nǹkan mímọ́, ó tún òfin Ọlọ́run sọ lọ́nà yìí: “Kí ẹnikẹ́ni má ṣe ṣáátá òrìṣà táwọn ìlú mìíràn ń bọ, bẹ́ẹ̀ ni kí wọ́n má ṣe ja àwọn tẹ́ńpìlì ilẹ̀ òkèèrè lólè, kí wọ́n má sì lọ kó ìṣúra tí wọ́n ti yà sí mímọ́ fún òrìṣà èyíkéyìí.” (Ìkọ̀wé wínníwínní jẹ́ tiwa.)—Jewish Antiquities, Ìwé Kẹrin, orí kẹjọ, ìpínrọ̀ kẹwàá.