Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Ọmọ Rúbẹ́nì ni Dátánì àti Ábírámù tó bá Kórà lẹ̀dí àpò pọ̀. Fún ìdí yìí, kò jọ pé ipò àlùfáà làwọn ń dù. Ní tiwọn, ohun tó ń bí wọn nínú ni jíjẹ́ tí Mósè jẹ́ aṣáájú lórí wọn, àti bó ṣe jẹ́ pé títí dìgbà yẹn, wọn ò tíì dé Ilẹ̀ Ìlérí tí wọ́n ń lọ.—Númérì 16:12-14.