Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Fi wé ìtàn tó wà nínú 1 Sámúẹ́lì 1:3, 7. Níbẹ̀, “nígbàkúùgbà” (nínú ìtumọ̀ èdè Hébérù òde òní) ń tọ́ka sí ìṣẹ̀lẹ̀ tó máa ń wáyé “lọ́dọọdún,” tàbí lẹ́ẹ̀kan lọ́dún, nígbà tí Ẹlikénà àti àwọn aya rẹ̀ méjèèjì bá lọ sí àgọ́ ìjọsìn ní Ṣílò.