Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Láti ṣàṣàrò tàdúràtàdúrà lórí ibi tó o kà nínú Bíbélì, o lè béèrè lọ́wọ́ ara rẹ pé: ‘Ǹjẹ́ ibí yìí sọ ọ̀kan tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ lára àwọn ànímọ́ Jèhófà fún mi? Báwo ló ṣe bá àkòrí Bíbélì mu? Báwo ni mo ṣe lè lò ó nínú ìgbésí ayé mi tàbí kí n fi ran àwọn ẹlòmíràn lọ́wọ́?’