Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Lóòótọ́ ni àwọn ẹ̀ka àjàrà náà ń tọ́ka sí àwọn àpọ́sítélì Jésù àtàwọn Kristẹni mìíràn tí wọ́n máa nípìn-ín nínú Ìjọba ọ̀run ti Ọlọ́run, àmọ́ gbogbo àwọn ọmọ ẹ̀yìn Kristi lóde òní ló lè jàǹfààní nínú òtítọ́ tó wà nínú àkàwé náà.—Jòhánù 3:16; 10:16.