Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Bí ọ̀ràn bá dójú ẹ̀ nígbà mìíràn, ó lè di dandan kí ọkọ àti aya pínyà. (1 Kọ́ríńtì 7:10, 11; wo ìwé Àṣírí Ayọ̀ Ìdílé, ojú ìwé 160 sí 161, àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà la tẹ̀ ẹ́ jáde.) Láfikún sí i, Bíbélì fàyè gba ìkọ̀sílẹ̀ bí ọ̀kan lára wọn bá ṣàgbèrè (ìyẹn bí ọ̀kan lára wọn bá lọ ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ẹlòmíràn).—Mátíù 19:9.