Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Àpọ́sítélì Pétérù fi ipò ìtanù nípa tẹ̀mí yìí wé bí ìgbà téèyàn wà nínú “ẹ̀wọ̀n.” Àmọ́ ṣá, kì í ṣe “ọ̀gbun àìnísàlẹ̀” tí a ó sọ àwọn ẹ̀mí èṣù sí fún ẹgbẹ̀rún ọdún ni Pétérù ń sọ o.—1 Pétérù 3:19, 20; Lúùkù 8:30, 31; Ìṣípayá 20:1-3.