Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Bíbélì fúnra rẹ̀ fi hàn pé Jerúsálẹ́mù ṣubú ní àádọ́rin ọdún ṣáájú ìgbà tí àwọn Júù tá a kó ní ìgbèkùn padà dé ní ọdún 537 ṣáájú Sànmánì Tiwa. (Jeremáyà 25:11, 12; Dáníẹ́lì 9:1-3) Fún àlàyé kíkún lórí “àwọn àkókò tí a yàn kalẹ̀ fún àwọn orílẹ̀-èdè,” wo ojú ìwé 95 sí 97 nínú ìwé Reasoning From the Scriptures, tí àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà tẹ̀ jáde.