Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Àwọn ẹsẹ mìíràn nínú Ìwé Mímọ́ Kristẹni Lédè Gíríìkì tún fi hàn pé Jésù ni Ẹni Àmì Òróró Ọlọ́run tá a tọ́ka sí nínú sáàmù kejì. Èyí hàn kedere nígbà tá a fi Sáàmù 2:7 wéra pẹ̀lú Ìṣe 13:32, 33 àti Hébérù 1:5; 5:5. Tún wo Sáàmù 2:9; àti Ìṣípayá 2:27.