Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Ó jọ pé Jòhánù nìkan ló gbọ́ ohùn Ọlọ́run nígbà ìrìbọmi Jésù. Àwọn Júù tí Jésù bá sọ̀rọ̀ “kò tíì gbọ́ ohùn [Ọlọ́run] nígbà kankan rí, bẹ́ẹ̀ ni [wọn] kò tíì rí ìrísí rẹ̀.”—Jòhánù 5:37.
a Ó jọ pé Jòhánù nìkan ló gbọ́ ohùn Ọlọ́run nígbà ìrìbọmi Jésù. Àwọn Júù tí Jésù bá sọ̀rọ̀ “kò tíì gbọ́ ohùn [Ọlọ́run] nígbà kankan rí, bẹ́ẹ̀ ni [wọn] kò tíì rí ìrísí rẹ̀.”—Jòhánù 5:37.