Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Ní ṣáńgílítí, ohun tí ọ̀rọ̀ Gíríìkì ìpilẹ̀ṣẹ̀ tá a tú sí “ìroragógó wàhálà” túmọ̀ sí ni “ìrora ìrọbí.” (Mátíù 24:8, Kingdom Interlinear) Èyí fi hàn pé bí ìrora aláboyún ṣe máa ń le sí i nígbà tó bá ń rọbí, tí kò ní dáwọ́ dúró, bẹ́ẹ̀ náà ni ìṣòro ayé yìí yóò ṣe máa le sí i títí yóò fi jálẹ̀ sí ìpọ́njú ńlá.