Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Tí a bá yọ lẹ́tà kan kúrò nínú ẹsẹ Bíbélì yẹn lédè Hébérù, ó lè kà pé “ó fi wọ́n sínú ayùn” tàbí “ó (fi ayùn) rẹ́ wọn sí wẹ́wẹ́.” Síwájú sí i, ọ̀rọ̀ náà tá a túmọ̀ sí “ibi tí wọ́n ti ń sun bíríkì” tún lè túmọ̀ sí “ohun tí wọ́n fi ń yọ bíríkì.” Àmọ́, inú ohun tí wọ́n fi ń yọ bíríkì kéré jù ibi téèyàn lè gba kọjá lọ.