Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Bíi ti ará Etiópíà yìí làwọn ẹgbẹ̀ẹ́dógún Júù àtàwọn aláwọ̀ṣe Júù tó fetí sí ọ̀rọ̀ Pétérù ní ọjọ́ Pẹ́ńtíkọ́sì ṣe ṣèrìbọmi láìjáfara rárá. Àmọ́ ṣá o, àwọn náà ti mọ̀ nípa ẹ̀kọ́ àti ìlànà Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run ṣáájú àkókò yẹn bíi ti ìwẹ̀fà ará Etiópíà yẹn.—Ìṣe 2:37-41.