Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Nígbà ẹbọ fífì tí wọ́n máa ń lo ìṣù búrẹ́dì méjì fún yìí, àlùfáà sábà máa ń kó àwọn búrẹ́dì náà sí àtẹ́lẹwọ́ rẹ̀, á gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè, á sì máa fi àwọn búrẹ́dì náà sọ́tùn-ún àti sósì. Bó ṣe ń fi àwọn búrẹ́dì wọ̀nyí ń ṣàpẹẹrẹ fífún tí wọ́n fún Jèhófà láwọn ohun tí wọ́n fi rúbọ náà.—Wo ìwé Insight on the Scriptures, Ìdìpọ̀ Kejì, ojú ìwé 528. Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà la tẹ̀ ẹ́ jáde.