Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b A lè rí àwọn ohun tó jẹ mọ́ òfin, tí Mósè ṣàkọsílẹ̀ rẹ̀, nínú Ẹ́kísódù 24:4, 7; 34:27, 28; àti Diutarónómì 31:24-26. Bákan náà, Diutarónómì 31:22 sọ pé ó ṣàkọsílẹ̀ orin kan, àkọsílẹ̀ rẹ̀ nípa bí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ṣe ń lọ láti ibì kan sí ibòmíràn nínú aginjù wà nínú Númérì 33:2.