Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Bó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn Júù tó gbé ayé ní ọ̀rúndún kìíní Sànmánì Kristẹni ń rò pé Ọlọ́run máa ṣojúure sáwọn, nítorí pé àwọ́n jẹ́ àtọmọdọ́mọ Ábúráhámù, wọ́n ń retí ẹnì kan tó máa wá gẹ́gẹ́ bíi Mèsáyà tàbí Kristi.—Jòh. 1:25; 7:41, 42; 8:39-41.