Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Wọ́n fi ọ̀kan lára àwọn ẹyẹ wọ̀nyẹn ṣe ọrẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀. (Léfítíkù 12:6, 8) Bí Màríà sì ṣe rú ọrẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ yìí jẹ́ ká rí i pé, ó gbà pé bíi ti gbogbo èèyàn aláìpé tó kù, òun náà ti jogún ẹ̀ṣẹ̀ àtàwọn nǹkan tí ẹ̀ṣẹ̀ ń fà látọ̀dọ̀ Ádámù, ọkùnrin àkọ́kọ́.— Róòmù 5:12.