ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

c Àwọn èèyàn ti kíyè sí pé ó nídìí táwọn ìwé Ìhìn Rere ò fi dárúkọ Jósẹ́fù rárá nínú àkọsílẹ̀ tí wọ́n ṣe nípa iṣẹ́ òjíṣẹ́ Jésù, torí pé wọ́n dárúkọ ìyá ẹ̀, wọ́n dárúkọ àwọn àbúrò ẹ̀ lọ́kùnrin, wọ́n sì sọ̀rọ̀ nípa àwọn àbúrò ẹ̀ obìnrin. Bí àpẹẹrẹ, níbi ìgbéyàwó tó wáyé ní Kánà, ẹ̀rí wà pé ńṣe ni Màríà ń forí ṣe fọrùn ṣe níbi ìnáwó náà, àmọ́ àkọsílẹ̀ náà ò sọ̀rọ̀ nípa Jósẹ́fù rárá. (Jòhánù 2:1-11) Lásìkò tó yàtọ̀ séyìí, a kà pé “ọmọkùnrin Màríà” làwọn aráàlú Jésù ń pè é, wọn ò pè é ní ọmọkùnrin Jósẹ́fù.—Máàkù 6:3.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́