Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Nǹkan bí ogójì [40] ìgbà ni gbólóhùn náà “ọmọdékùnrin aláìníbaba” fara hàn nínú Bíbélì. Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọmọdékùnrin ni èdè Hébérù yẹn túmọ̀ sí lédè Yorùbá, àmọ́ ká má lọ rò pé ìlànà yẹn ò kan àwọn ọmọdébìnrin tí bàbá wọn ti kú o. Òfin Mósè jẹ́ ká mọ̀ pé àwọn ọmọdébìnrin aláìníbaba lẹ́tọ̀ọ́ tiwọn náà.—Númérì 27:1-8.