Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Òfin Mẹ́wàá àti Àdúrà Olúwa ni apá ibi tí wọ́n kọ́kọ́ fi ẹ̀rọ tẹ̀ nínú Bíbélì ní èdè Malagásì, erékùṣù Mauritius ni wọ́n ti tẹ̀ ẹ́ ní nǹkan bí oṣù April sí May ọdún 1826. Àmọ́ kìkì ìdílé Radama Ọba àti àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba díẹ̀ ní wọ́n pín in fún.