Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Ọ̀rọ̀ náà “ìwé onímìísí” ń tọ́ka sí àkójọ àwọn ìwé Bíbélì tí wọ́n ní ẹ̀rí tó dájú pé Ọlọ́run mí sí wọn. Àwọn ìwé mẹ́rìndínláàádọ́rin [66] ló wà táwọn èèyàn gbà pé wọ́n jẹ́ ìwé tó ní ìmísí Ọlọ́run tí wọ́n sì para pọ̀ di Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.