Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ọ̀rọ̀ náà, “òbí tó ń dá tọ́mọ” kò sí nínú Bíbélì, àmọ́ wọ́n sábà máa ń lo ọ̀rọ̀ náà, “opó” àti “ọmọdékùnrin aláìníbaba” nínú rẹ̀. Èyí fi hàn pé, àwọn òbí tó ń dá tọ́mọ wọ́pọ̀ lákòókò tí wọ́n ń kọ Bíbélì.—Aísáyà 1:17.