Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Ọ̀pọ̀ èèyàn mọ gbólóhùn náà, “OLÚWA ni Olùṣọ́ Àgùntàn mi.” Láti mọ ìdí tí àwọn ìtúmọ̀ Bíbélì kan fi yọ Jèhófà tó jẹ́ orúkọ Ọlọ́run kúrò nínú Bíbélì, ka ìwé Kí Ni Bíbélì Fi Kọ́ni Gan-an? lójú ìwé 195 sí 197. Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà la ṣe é.