Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Léfì ṣiṣẹ́ nínú tẹ́ńpìlì ní ọjọ́ Sábáàtì síbẹ̀ ‘wọ́n ń bá a lọ láìjẹ̀bi.’ Ọlọ́run ti yan Jésù ṣe àlùfáà àgbà nínú tẹ́ńpìlì ńlá nípa tẹ̀mí. Torí náà, òun pẹ̀lú lè ṣe iṣẹ́ tẹ̀mí tí Ọlọ́run yàn fún un ní ọjọ́ Sábáàtì láìbẹ̀rù pé òun máa rú òfin Sábáàtì.—Mát. 12:5, 6.