Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Ọ̀rọ̀ tí Pọ́ọ̀lù sọ yìí tún àsọtẹ́lẹ̀ àkọ́kọ́ tó wà nínú Bíbélì sọ, ìyẹn Jẹ́nẹ́sísì 3:15, tó sọ nípa bí Èṣù ṣe máa pa run níkẹyìn. Pọ́ọ̀lù lo àwọn ọ̀rọ̀ Gíríìkì tó túmọ̀ sí “fọ́ sí wẹ́wẹ́, rún wómúwómú” láti ṣàlàyé ìṣẹ̀lẹ̀ náà.—Vine’s Complete Expository Dictionary of Old and New Testament Words.