Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Ọ̀rọ̀ ìpilẹ̀ṣẹ̀ tá a túmọ̀ sí “pàǹtírí” nínú ẹsẹ yìí tún túmọ̀ sí “ẹlẹ́bọ́tọ,” “ìgbọ̀nsẹ̀” tàbí, “ohun tá a jù sí àwọn ajá.” Ọ̀mọ̀wé nípa Bíbélì kan sọ pé bí Pọ́ọ̀lù ṣe lo ọ̀rọ̀ yìí fi hàn pé ó “kẹ̀yìn sí ohunkóhun tí kò ní láárí tó sì ń kóni nírìíra tí èèyàn kò fẹ́ ní nǹkan kan ṣe pẹ̀lú rẹ̀ mọ́.”