Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Bó tilẹ̀ jẹ́ pé orúkọ yẹn fara hàn nínú Ìwé Mímọ́ lédè Hébérù, èyí táwọn kan ń pè ní Májẹ̀mú Láéláé, ó yani lẹ́nu pé àwọn kan dìídì yọ orúkọ Ọlọ́run kúrò nínú ọ̀pọ̀ Bíbélì. Wọ́n wá fi àwọn orúkọ oyè bí “Olúwa” tàbí “Ọlọ́run” rọ́pò rẹ̀. Tó o bá fẹ́ mọ̀ sí i nípa ohun tá a sọ yìí, wo ojú ìwé 195 sí 197 nínú ìwé Kí Ni Bíbélì Fi Kọ́ni Gan-an? Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà la ṣe é.