ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

f Bákan náà, a ò gbọ́dọ̀ ní ohunkóhun ṣe pẹ̀lú ẹgbẹ́ èyíkéyìí tó ní ìsopọ̀ pẹ̀lú ẹ̀sìn èké, bí ẹgbẹ́ ọ̀dọ́ tàbí àwọn míì bẹ́ẹ̀, a kì í sì í lọ síbi eré ìdárayá tàbí ìmárale táwọn onísìn ṣètò. Bí àpẹẹrẹ, a lè rí àlàyé tó kún rẹ́rẹ́ nípa bóyá Kristẹni kan lè dara pọ̀ mọ́ àjọ YMCA (Young Men’s Christian Association) lábẹ́ “Ìbéèrè Láti Ọwọ́ Àwọn Òǹkàwé” nínú Ilé Ìṣọ́ August 1, 1979. Ìlànà kan náà ló kan àjọ YWCA (Young Women’s Christian Association). Bó tiẹ̀ jẹ́ pé àwọn kan lè sọ pé kò fi bẹ́ẹ̀ sọ́rọ̀ tó jẹ mọ́ ẹ̀sìn nínú àwọn ẹgbẹ́ yìí, síbẹ̀ ìwádìí fi hàn pé àwọn ẹlẹ́sìn ló dá wọn sílẹ̀, ọ̀rọ̀ ẹ̀sìn ni wọ́n sì ń gbé lárugẹ.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́