Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Màríà mọ Ìwé Mímọ́ dáadáa, ó sì máa ń fa ọ̀rọ̀ yọ látinú ẹ̀. (Lúùkù 1:46-55) Ó jọ pé Jósẹ́fù àti Màríà ò lówó tí wọ́n lè fi ra àwọn Ìwé Mímọ́ tiwọn. Ó dájú pé wọ́n á máa tẹ́tí sílẹ̀ gan-an tí wọ́n bá ń ka Ìwé Mímọ́ nínú sínágọ́gù, kí wọ́n lè máa rántí ẹ̀ tó bá yá.