Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Bíbélì tún jẹ́ ká mọ̀ pé Jèhófà máa ń ṣe àwọn nǹkan kan “nítorí orúkọ rẹ̀.” Bí àpẹẹrẹ, ó máa ń darí àwọn èèyàn ẹ̀, ó máa ń ràn wọ́n lọ́wọ́, ó máa ń gbà wọ́n sílẹ̀, ó máa ń dárí jì wọ́n, ó sì máa ń dáàbò bò wọ́n. Jèhófà máa ń ṣe gbogbo nǹkan yìí nítorí orúkọ rẹ̀.—Sm. 23:3; 31:3; 79:9; 106:8; 143:11.